Additional Information

Additional Information

Account Navigation

Account Navigation

Currency - All prices are in AUD

Currency - All prices are in AUD
 Loading... Please wait...
Africa World Press & The Red Sea Press

ÌLÒ ÈDÈ ÀTI ÈDÁ ÈDE YORÙBÁ: APÁ KEJÌ Yorùbá Linguistics and Language Use: Part Two, Edited by Harrison Adéníyì and Akinloyè Òjó

$24.95

ÌLÒ ÈDÈ ÀTI ÈDÁ ÈDE YORÙBÁ: APÁ KEJÌ Yorùbá Linguistics and Language Use: Part Two, Edited by Harrison Adéníyì and Akinloyè Òjó

$24.95
SKU:
9781592213641
Quantity:
Share

Product Description

Ìfë tí àwön ènìyàn fi hàn sí apá kìíní àti ôpôlöpô ôrô ìyànjú tí wõn gbà wá ló gún wa ní kësë, ló sì ýe okùnfà ìwé yìí tí í ýe Ìlò Èdè àti Êdá-Èdè Yorùbá (Apá Kejì).

Nínú apá kejì yìí, a tanná wò lára àwön àkórí tí kò sí nínú apá kìíní, ýùgbõn tí a lérò pé ó wúlò fún àwön akëkôõ èdè Yorùbá ní ilé-êkõ olùkõni Ën-Siì, Yunifásitì gbogbo tí wõn ti  kõ èdè Yorùbá àti àwön olùkôõ tí wõn fë ta ìmô wön jí nínú êkõ èdè Yorùbá.

A gbìyànjú láti tanná wo díê lára àwön tíõrì tí yóò wúlò fún akëkôõ èdè Yorùbá. Lára àwön tíõrì yìí ni ti síÂtáàsì àti ti fonõlõjì. A tún wo abala êkõ tí ó dàbí çni pé wön kò ì tíì mënu bà ní èdè Yorùbá. Èyí ni ìmô êdá-èdè ajçmáwùjö àti sêmáÂtíìkì. Gëgë bí a ti sö nípa apá kìíní, àkójöpô àwön ìwé ìlëwõ tí a ti  fi kõ àwön ömö wa fún ödún díê sëyìn ní ìlò èdè àti ìmô êdá-èdè Yorùbá ni a pa pô tí a tún ýe àtúnýe díê tí ó di ìwé yìí

ÌLÒ ÈDÈ ÀTI ÈDÁ ÈDE YORÙBÁ: APÁ KEJÌ (Yorùbá Linguistics and Language Use: Part Two) is the second installment of the collection of works on the form and function of the Yoruba language. The twelve chapters in the book focus on various aspects of Yorùbá language and linguistics. These include the discussion of current theoretical trends in syntax, grammar and phonology as they relate to the Yorùbá language. In addition, the book includes chapters on Yorùbá semantics and sociolinguistics, areas often overlooked in works on Yoruba language studies. In going beyond the scope of the first collection, ÌLÒ ÈDÈ ÀTI ÈDÁ ÈDE YORÙBÁ: APÁ KEJÌ includes chapters on the comparative analysis of Yorùbá and other Nigerian languages as well as the relationship between Yorùbá linguistics and literature.

ABOUT THE EDITORS
Harrison Adéníyì is a Senior Lecturer in the Department of African Languages and Literature, Lagos State University, Lagos, Nigeria. He teaches Linguistics and Yorùbá language courses. Adéníyì trained at the University of Ibadan, Ibadan, Nigeria. Some of his published books include: Language and Communication: An Introductory Text. Volume 1(1999); Ìlò-Èdè àti Èdá-Ède Yorùbá: Apá Kínní (2000). His articles on Yorùbá and Edo Linguistics have appeared in several scholarly journals. He is currently the National treasurer of Linguistics Association of Nigeria.

Akinloyè Òjó is an assistant professor in the Department of Comparative Literature and the African Studies Institute at the University of Georgia. He teaches Yorùbá and African Studies courses in both. His research is in the areas of African language pedagogy, material development language teaching, and language and linguistic research in Yorùbá. His published works include: The Active Yorùbá Classroom: In-Class Situations for Yorùbá Language Instruction and Practice (2003); The Challenges and Methodologies of African Language Instruction in the West/United States (2002); and In Flight: A Collection of Poems (2000). He is currently the Executive Editor for the African Language Teachers’ Association (ALTA).

CATEGORY
Linguistics, Language Studies/AFRICA

Product Reviews

Find Similar Products by Category